1Yin Olúwa, ìwọ ọkàn mi; àti gbogbo ohun tí ó wà nínú mi, yín orúkọ rẹ̀ mímọ́.
2Yin Olúwa, ìwọ ọkàn mi, kí o má ṣe gbàgbé gbogbo oore rẹ̀,
3ẹni tí ó dárí gbogbo ẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀ jì ọ́
4ẹni tí ó ra ẹ̀mí rẹ padà kúrò nínú kòtò ikú
5ẹni tí ó fi ohun dídára tẹ́ ọ lọ́rùn
6Olúwa ń ṣe òdodo àti ìdájọ́ fún
7Ó fi ọ̀nà rẹ̀ hàn fún Mose, iṣẹ́ rẹ̀ fun àwọn ọmọ Israẹli;
8Olúwa ni aláàánú àti olóore,
9Òun kì í bá ni wí ní ìgbà gbogbo
10Òun kì í ṣe sí wa gẹ́gẹ́ bí ẹ̀ṣẹ̀ wa
11Nítorí bí ọ̀run ṣe ga sílẹ̀,
12Bí ìlà-oòrùn ti jìnnà sí ìwọ̀-oòrùn
13Bí baba ti ń ṣe ìyọ́nú sí àwọn ọmọ rẹ̀,
14nítorí tí ó mọ dídá wa,
15Bí ó ṣe ti ènìyàn ni, ọjọ́ rẹ̀ dàbí koríko,
16afẹ́fẹ́ fẹ́ kọjá lọ lórí rẹ̀,
17Ṣùgbọ́n láti ayérayé ni ìfẹ́
18sí àwọn tí ó pa májẹ̀mú rẹ̀ mọ́
19Olúwa ti pèsè ìtẹ́ rẹ̀ nínú ọ̀run,
20Yin Olúwa, ẹ̀yin angẹli rẹ̀,
21Yin Olúwa, ẹ̀yin ogun ọ̀run rẹ̀ gbogbo,
22Yin Olúwa, gbogbo iṣẹ́ rẹ̀ ní