1Olúwa kórìíra òsùwọ̀n èké,
2Nígbà tí ìgbéraga bá dé, nígbà náà ni ìdójútì dé,
3Òtítọ́ inú ẹni dídúró ṣinṣin ń ṣe amọ̀nà rẹ̀,
4Ọ̀rọ̀ kò níláárí ní ọjọ́ ìbínú,
5Òdodo aláìlẹ́gàn ṣe ọ̀nà tààrà fún wọn,
6Òdodo ẹni ìdúró ṣinṣin gbà wọ́n là,
7Nígbà tí ènìyàn búburú bá kú, ìrètí rẹ̀ a parun;
8A gba olódodo kúrò lọ́wọ́ ibi dípò o rẹ̀,
9Aláìmọ Ọlọ́run fi ẹnu rẹ̀ ba aládùúgbò rẹ̀ jẹ́,
10Nígbà tí olódodo ń gbèrú, ìlú a yọ̀;
11Nípasẹ̀ ìbùkún, olódodo a gbé ìlú ga:
12Ẹni tí kò gbọ́n fojú kékeré wo aládùúgbò rẹ̀
13Olófòófó tú àṣírí ìkọ̀kọ̀
14Nítorí àìní ìtọ́sọ́nà orílẹ̀-èdè ṣubú
15Ẹni tí ó ṣe onígbọ̀wọ́ fún àlejò yóò rí ìyọnu,
16Obìnrin oníwà rere gba ìyìn
17Ènìyàn rere ń ṣe ara rẹ̀ lóore
18Ènìyàn búburú gba èrè ìtànjẹ
19Olódodo tòótọ́ rí ìyè
20Olúwa kórìíra àwọn ènìyàn ọlọ́kàn búburú
21Mọ èyí dájú pé, ènìyàn búburú kì yóò lọ láìjìyà,
22Bí òrùka wúrà ní imú ẹlẹ́dẹ̀
23Ìfẹ́ inú olódodo yóò yọrí sí ohun rere
24Ènìyàn kan ń fún ni lọ́fẹ̀ẹ́, síbẹ̀ ó ń ní sí i;
25Ẹni tí ń ṣoore yóò máa gbèrú sí i;
26Àwọn ènìyàn a ṣẹ́ èpè lé ènìyàn tí ń kó oúnjẹ pamọ́
27Ẹni tí ń lépa ohun rere yóò rí ohun rere
28Ẹnikẹ́ni tí ó bá gbẹ́kẹ̀lé ọrọ̀ rẹ̀ yóò ṣubú;
29Ẹni tí ó ń mú ìdààmú dé bá ìdílé rẹ̀ yóò jogún afẹ́fẹ́ lásán
30Èso òdodo ni igi ìyè
31Bí àwọn olódodo bá gba ìpín wọn lórí ilẹ̀ ayé