1Àwọn òwe Solomoni.
2Ìṣúra tí a kójọ nípa ìwà búburú kò ní èrè,
3Olúwa kì í jẹ́ kí ebi máa pa olódodo,
4Ọwọ́ tí ó lẹ máa ń sọ ènìyàn di tálákà,
5Ẹni tí ó kó irúgbìn jọ ní àsìkò òjò jẹ́ ọlọ́gbọ́n ọmọ,
6Ìbùkún ní ó máa ń kún orí olódodo,
7Ìrántí olódodo yóò jẹ́ ìbùkún,
8Ẹni tí ó gbọ́n nínú ọkàn rẹ̀ máa ń gba àṣẹ,
9Ẹni tí ó ń rìn déédé, ń rìn láìléwu,
10Ẹni tí ń ṣẹ́jú pàkòpàkò fún ibi ń fa àìbalẹ̀ ọkàn,
11Ẹnu olódodo jẹ́ orísun ìyè,
12Ìríra a máa dá ìjà sílẹ̀,
13Ọgbọ́n ni a ń bá lẹ́nu àwọn olóye,
14Ọlọ́gbọ́n ènìyàn kó ìmọ̀ jọ,
15Ọrọ̀ àwọn olódodo ni ìlú olódi wọn,
16Èrè olódodo ń mú ìyè wá fún wọn,
17Ẹni tí ó gbọ́ ìbáwí fi ọ̀nà sí ìyè hàn,
18Ẹni tí ó pa ìkórìíra rẹ̀ mọ́ jẹ́ òpùrọ́
19Nínú ọ̀rọ̀ púpọ̀ a kò le fẹ́ ẹ̀ṣẹ̀ kù
20Ètè olódodo jẹ́ ààyò fàdákà,
21Ètè olódodo ń bọ́ ọ̀pọ̀lọpọ̀,
22Ìbùkún Olúwa ń mú ọrọ̀ wá,
23Aláìgbọ́n a máa ní inú dídùn sí ìwà búburú,
24Ohun tí ènìyàn búburú bẹ̀rù yóò dé bá a;
25Nígbà tí ìjì bá ti jà kọjá, ènìyàn búburú a kọjá lọ,
26Bí ọtí kíkan sí eyín, àti èéfín sí ojú,
27Ìbẹ̀rù Olúwa ń mú ọjọ́ ayé gígùn wá,
28Ìrètí olódodo ni ayọ̀,
29Ọ̀nà Olúwa jẹ́ ààbò fún olódodo,
30A kì yóò fa olódodo tu láéláé,
31Ẹnu olódodo ń mú ọgbọ́n jáde wá,
32Ètè olódodo mọ ohun ìtẹ́wọ́gbà,