1Ìgbà náà ni Bilidadi, ará Ṣuhi, sì dáhùn wí pé,
2“Ìwọ yóò ti máa sọ nǹkan wọ̀nyí pẹ́ tó?
3Ọlọ́run a ha máa yí ìdájọ́ po bí?
4Nígbà tí àwọn ọmọ rẹ̀ ṣẹ̀ sí i,
5Bí ìwọ bá sì ké pe Ọlọ́run ní àkókò,
6Ìwọ ìbá jẹ́ mímọ, kí ó sì dúró ṣinṣin:
7Ìpilẹ̀ṣẹ̀ rẹ ìbá tilẹ̀ kéré si í,
8“Èmi bẹ̀ ọ́ ǹjẹ́, béèrè lọ́wọ́ àwọn ará ìgbà nì
9Nítorí pé ọmọ-àná ni àwa, a kò sì mọ nǹkan,
10Àwọn kì yóò wa kọ ọ́, wọn kì yóò sì sọ fún ọ?
11Papirusi ha lè dàgbà láìní ẹrẹ̀
12Nígbà tí ó wà ní tútù, tí a kò ké e lulẹ̀,
13Bẹ́ẹ̀ ni ipa ọ̀nà gbogbo àwọn tí ó gbàgbé Ọlọ́run,
14Àbá ẹni tí a ó kèé kúrò,
15Yóò fi ara ti ilé rẹ̀, ṣùgbọ́n kì yóò lè dúró,
16Ó tutù bí irúgbìn tí a bomirin níwájú oòrùn,
17Gbòǹgbò rẹ̀ ta yí ebè ká,
18Bí ó bá sì pa á run kúrò ní ipò rẹ̀,
19Kíyèsi i, ayé rẹ̀ gbẹ dànù
20“Kíyèsi i, Ọlọ́run kì yóò ta ẹni òtítọ́ nù,
21títí yóò fi fi ẹ̀rín kún ọ ní ẹnu,
22ìtìjú ní a o fi bo àwọn tí ó kórìíra rẹ̀,