1“Ẹ̀mí mi bàjẹ́,
2Nítòótọ́ àwọn ẹlẹ́yà wà lọ́dọ̀ mi,
3“Fi fún mi Olúwa, ìlérí tí ìwọ fẹ́;
4Nítorí pé ìwọ ti sé wọ́n láyà kúrò nínú òye;
5Ẹni tí ó sọ ọ̀rọ̀ ẹ̀tàn dídún fún àwọn ọ̀rẹ́ rẹ̀ fún èrè,
6“Ọlọ́run ti sọ mi di ẹni òwe fún àwọn ènìyàn;
7Ojú mí ṣú bàìbàì nítorí ìbìnújẹ́,
8Àwọn olódodo yóò yanu sí èyí,
9Olódodo pẹ̀lú yóò di ọ̀nà rẹ̀ mú,
10“Ṣùgbọ́n bí ó ṣe ti gbogbo yín,
11Ọjọ́ tí èmi ti kọjá, ìrò mi ti fà yá,
12Àwọn ènìyàn wọ̀nyí ń ṣọ́ òru di ọ̀sán;
13Bí mo tilẹ̀ ní ìrètí, ipò òku ní ilé mi;
14Èmi ti wí fún ìdíbàjẹ́ pé, ìwọ ni baba mi,
15ìrètí mi ha dà nísinsin yìí?
16Yóò sọ̀kalẹ̀ lọ sínú ipò òkú,