1Gbọ́ ọ̀rọ̀ tí Olúwa sọ fún yín ẹ̀yin ilé Israẹli.
2Báyìí ni Olúwa wí:
3Nítorí pé asán ni àṣà àwọn ènìyàn,
4Wọ́n fi fàdákà àti wúrà ṣe é lọ́ṣọ̀ọ́.
5Wọ́n wé mọ́ igi bí ẹ̀gúnsí inú oko,
6Kò sí ẹni tí ó dàbí rẹ Olúwa;
7Ta ni kò yẹ kí ó bẹ̀rù rẹ?
8Gbogbo wọn jẹ́ aláìlóye àti aṣiwèrè,
9Fàdákà tí a ti kàn ni a mú wá láti Tarṣiṣi,
10Ṣùgbọ́n Olúwa ni Ọlọ́run tòótọ́,
11“Sọ èyí fún wọn: ‘Àwọn ọlọ́run kéékèèké tí kò dá ọ̀run àti ayé ni yóò ṣègbé láti ayé àti ní abẹ́ ọ̀run.’ ”
12Ọlọ́run dá ayé pẹ̀lú agbára rẹ̀,
13Nígbà tí ó bá sán àrá, àwọn omi lọ́run a sì pariwo;
14Gbogbo ènìyàn jẹ́ aṣiwèrè àti aláìnímọ̀,
15Asán ni wọ́n, iṣẹ́ ìṣìnà;
16Ẹni tí ó bá jẹ́ ìpín Jakọbu kò sì dàbí èyí,
17Kó ẹrù rẹ kúrò láti fi ilẹ̀ náà sílẹ̀
18Nítorí èyí ni Olúwa wí:
19Ègbé ni fún mi nítorí ìpalára mi!
20Àgọ́ mi bàjẹ́,
21Àwọn olùṣọ́-àgùntàn jẹ́ aṣiwèrè,
22Fetísílẹ̀! ariwo igbe ń bọ̀,
23Èmi mọ̀ Olúwa wí pé ọ̀nà ènìyàn kì í ṣe ti ara rẹ̀,
24Tún mi ṣe Olúwa, pẹ̀lú ìdájọ́ nìkan
25Tú ìbínú rẹ jáde sórí àwọn orílẹ̀-èdè