1Nígbà náà ní Bilidadi, ará Ṣuhi, dáhùn wí pé,
2“Ìjọba àti ẹ̀rù ń bẹ lọ́dọ̀ Ọlọ́run rẹ̀,
3Àwọn ọmọ-ogun rẹ̀ ha ní ìyè bí,
4Èéha ti ṣe tí a ó fi dá ènìyàn láre lọ́dọ̀ Ọlọ́run?
5Kíyèsi i, òṣùpá kò sì lè tàn ìmọ́lẹ̀,
6kí a má sọ ènìyàn tí i ṣe ìdin,
Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní · iorubá
1Nígbà náà ní Bilidadi, ará Ṣuhi, dáhùn wí pé,
2“Ìjọba àti ẹ̀rù ń bẹ lọ́dọ̀ Ọlọ́run rẹ̀,
3Àwọn ọmọ-ogun rẹ̀ ha ní ìyè bí,
4Èéha ti ṣe tí a ó fi dá ènìyàn láre lọ́dọ̀ Ọlọ́run?
5Kíyèsi i, òṣùpá kò sì lè tàn ìmọ́lẹ̀,
6kí a má sọ ènìyàn tí i ṣe ìdin,