1“Sọ̀kalẹ̀, jókòó nínú eruku,
2Mú òkúta-ọlọ kí o sì lọ ìyẹ̀fun;
3Ìhòhò rẹ ni a ó sí síta
4Olùràpadà wa Olúwa àwọn ọmọ-ogun ni orúkọ rẹ̀
5“Jókòó ní ìdákẹ́ jẹ́ẹ́, lọ sínú òkùnkùn,
6Inú bí mi sí àwọn ènìyàn mi
7Ìwọ wí pé, ‘Èmi yóò tẹ̀síwájú títí láé—
8“Nísinsin yìí, tẹ́tí sílẹ̀, ìwọ oníwọ̀ra ẹ̀dá
9Méjèèjì yìí ni yóò wá sórí rẹ
10Ìwọ ti ní ìgbẹ́kẹ̀lé nínú ìwà ìkà rẹ
11Ìparun yóò dé bá ọ
12“Tẹ̀síwájú nígbà náà, pẹ̀lú àfọ̀ṣẹ rẹ
13Gbogbo ìmọ̀ràn tí o ti gbà ni
14Lóòótọ́ wọ́n dàbí ìṣẹ́pẹ́ igi;
15Gbogbo ohun tí wọ́n lè ṣe fún ọ nìyìí