1“Èyí ni ohun tí Olúwa sọ fún ẹni òróró rẹ̀,
2Èmi yóò lọ síwájú rẹ,
3Èmi yóò sì fún ọ ní àwọn ọrọ̀ ibi òkùnkùn,
4Nítorí Jakọbu ìránṣẹ́ mi
5Èmi ni Olúwa, àti pé kò sí ẹlòmíràn;
6tí o fi jẹ́ pé láti ìlà-oòrùn
7Mo dá ìmọ́lẹ̀, mo sì dá òkùnkùn,
8“Ìwọ ọ̀run lókè rọ òjò òdodo sílẹ̀;
9“Ègbé ni fún ènìyàn tí ó ń bá Ẹlẹ́dàá rẹ̀ jà,
10Ègbé ni fún ẹni tí ó sọ fún baba rẹ̀ pé,
11“Ohun tí Olúwa wí nìyìí,
12Èmi ni ẹni tí ó dá ilẹ̀ ayé
13Èmi yóò gbé Kirusi sókè nínú òdodo mi.
14Ohun tí Olúwa wí nìyìí:
15Nítòótọ́ ìwọ jẹ́ Ọlọ́run tí ó fi ara rẹ̀ pamọ́,
16Gbogbo àwọn tí ó ń gbẹ́ ère ni ojú yóò tì
17Ṣùgbọ́n Israẹli ni a ó gbàlà láti ọwọ́ Olúwa
18Nítorí èyí ni ohun tí Olúwa wí,
19Èmi kò sọ̀rọ̀ níbi tí ó fi ara sin,
20“Ẹ kó ara yín jọ kí ẹ sì wá;
21Jẹ́ kí a mọ ohun tí yóò ṣẹlẹ̀, fihàn wá,
22“Yípadà sí mi kí a sì gbà ọ́ là,
23Nípa èmi tìkára mi ni mo ti búra,
24Wọn yóò sọ ní ti èmi, ‘Nínú Olúwa nìkan ni
25Ṣùgbọ́n nínú Olúwa gbogbo àwọn ìran Israẹli