1“Ṣùgbọ́n gbọ́ nísinsin yìí, ìwọ Jakọbu ìránṣẹ́ mi,
2Ohun tí Olúwa wí nìyìí
3Nítorí èmi yóò da omi sí ilẹ̀ tí ń pòǹgbẹ
4Wọn yóò dàgbàsókè gẹ́gẹ́ bí i koríko nínú pápá oko tútù,
5Ọ̀kan yóò wí pé, ‘Èmi jẹ́ ti Olúwa’;
6“Ohun tí Olúwa wí nìyìí
7Ta ni ó dàbí ì mi? Jẹ́ kí o kéde rẹ̀.
8Má ṣe wárìrì, má ṣe bẹ̀rù.
9Gbogbo àwọn tí ń gbẹ́ ère jásí asán,
10Ta ni ó mọ òrìṣà kan tí ó sì ya ère,
11Òun àti nǹkan rẹ̀ wọ̀nyí ni a ó dójútì;
12Alágbẹ̀dẹ mú ohun èlò,
13Gbẹ́nàgbẹ́nà fi ìwọ̀n wọ́n ọ́n
14Ó gé igi kedari lulẹ̀,
15Ohun èlò ìdáná ni fún ènìyàn;
16Ìlàjì igi náà ni ó jó nínú iná;
17Nínú èyí tí ó kù ni ó ti ṣe òrìṣà, ère rẹ̀;
18Wọn kò mọ nǹkan kan, nǹkan kan kò yé wọn;
19Kò sí ẹni tí ó dúró láti ronú,
20Ó ń jẹ eérú, ọkàn ẹlẹ́tàn ni ó ṣì í lọ́nà;
21“Rántí àwọn nǹkan wọ̀nyí, ìwọ Jakọbu,
22Èmi ti gbá gbogbo ìkùnà rẹ dànù bí i kurukuru,
23Kọrin fáyọ̀, ẹ̀yin ọ̀run, nítorí Olúwa ló ti ṣe èyí;
24“Ohun tí Olúwa wí nìyìí
25ta ni ó ba àmì àwọn wòlíì èké jẹ́
26ẹni tí ó gbé ọ̀rọ̀ àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀ jáde
27ta ni ó sọ fún omi jíjìn pé, ‘Ìwọ gbẹ,
28ta ni ó sọ nípa Kirusi pé, ‘Òun ni Olùṣọ́-àgùntàn mi