1Ègbé ni fún ọ, Arieli, Arieli,
2Síbẹ̀síbẹ̀ èmi yóò dó ti Arieli
3Èmi yóò sì wà ní bùba yí ọ ká níbi gbogbo,
4Ní ìrẹ̀sílẹ̀, ìwọ ó sì máa sọ̀rọ̀ láti ilẹ̀ wá;
5Ṣùgbọ́n àwọn ọ̀tá rẹ, yóò dàbí yanrìn kíkúnná,
6Olúwa àwọn ọmọ-ogun yóò wá
7Lẹ́yìn náà,
8àti bí ìgbà tí ẹni tí ebi ń pa ń lá àlá pé òun ń jẹun,
9Ẹ bẹ̀rù kí ẹnu kí ó yà yín,
10Olúwa ti mú oorun ìjìká wá sórí i yín:
11Fún un yín gbogbo ìran yìí kò yàtọ̀ sí àwọn ọ̀rọ̀ tí a fi èdìdì dì sínú ìwé kíká. Bí ẹ bá sì fún ẹni tí ó lè ka ìwé kíká náà, tí ẹ sì sọ fún un pé, “Jọ̀wọ́ ka èyí,” òun yóò dáhùn pé, “Èmi kò lè kà á; a ti dì í ní èdìdì.”
12Tàbí bí ẹ bá fún ẹni tí kò lè ka ìwé kíká náà tí ẹ sì sọ pé, “Jọ̀wọ́ ka èyí,” òun yóò dáhùn pé, “Èmi kò mọ̀ ọ́n kà.”
13Olúwa wí pé:
14Nítorí náà lẹ́ẹ̀kan sí i èmi yóò ya
15Ègbé ni fún àwọn tí ó lọ sí ọ̀gbun
16Ẹ̀yin dojú nǹkan délẹ̀,
17Ní àìpẹ́ jọjọ, ǹjẹ́
18Ní ọjọ́ náà adití yóò gbọ́ ọ̀rọ̀ ìwé kíká náà,
19Lẹ́ẹ̀kan sí i àwọn onírẹ̀lẹ̀ yóò yọ̀ nínú Olúwa:
20Aláìláàánú yóò pòórá,
21àwọn tí wọ́n fi ọ̀rọ̀ kan mú ẹnìkan di ẹlẹ́bi,
22Nítorí náà, èyí ni ohun tí Olúwa, ẹni tí ó ra Abrahamu padà sọ sí ilé Jakọbu:
23Nígbà tí wọ́n bá rí i láàrín àwọn ọmọ wọn,
24Gbogbo àwọn tí ń rìn ségesège ní yóò jèrè ìmọ̀;