1Ègbé ni fún adé ìgbéraga,
2Kíyèsi i, Olúwa ní ẹnìkan tí ó le, tí ó sì lágbára,
3Adé ìgbéraga àwọn ọ̀mùtí Efraimu,
4Òdòdó tí ó ń rọ náà tí í ṣe ẹwà ògo rẹ̀,
5Ní ọjọ́ náà Olúwa àwọn ọmọ-ogun
6Òun yóò sì jẹ́ ẹ̀mí ìdájọ́ òdodo
7Àwọn wọ̀nyí pẹ̀lú ta gbọ̀nọ́ngbọ̀nọ́n fún ọtí wáìnì
8Gbogbo orí tábìlì ni ó kún fún èébì
9“Ta ni ẹni náà tí ó ń gbìyànjú àti kọ́?
10Nítorí tí í ṣe: báyìí ni orí,
11Ó dára báyìí, pẹ̀lú ètè àjèjì àti ahọ́n àìmọ̀
12àwọn tí ó sọ fún wí pé,
13Fún ìdí èyí, ọ̀rọ̀ Olúwa sí wọn yóò di pé,
14Nítorí náà, ẹ gbọ́ ọ̀rọ̀ Olúwa, ẹ̀yin ẹlẹ́gàn,
15Ẹ fọ́n pé, “Àwa ti bá ikú mulẹ̀,
16Nítorí náà, báyìí ni Olúwa Olódùmarè wí:
17Èmi yóò fi ìdájọ́ ṣe okùn òsùwọ̀n
18Májẹ̀mú yín tí ẹ bá ikú dá ni a ó fa igi lé;
19Nígbàkígbà tí ó bá ti wá ni
20Ibùsùn kúrú púpọ̀ fún ìnara lé lórí,
21Olúwa yóò dìde sókè gẹ́gẹ́ bí ó ti ṣe
22Ní ìsinsin yìí ẹ dákẹ́ ẹlẹ́yà ṣíṣe,
23Tẹ́tí kí o sì gbọ́ ohùn mi,
24Nígbà tí àgbẹ̀ kan bá tu ilẹ̀ láti gbìn
25Nígbà tí òun bá ti tẹ́ ojú ilẹ̀ rẹ̀ pẹrẹsẹ
26Ọlọ́run rẹ̀ tọ́ ọ ṣọ́nà
27Nítorí a kò fi ohun èlò ìpakà dili,
28A gbọdọ̀ lọ ìyẹ̀fun kí a tó ṣe àkàrà;
29Gbogbo èyí pẹ̀lú ti ọ̀dọ̀ Olúwa àwọn ọmọ-ogun wá,