1Olúwa, ìwọ ni Ọlọ́run mi;
2Ìwọ ti sọ ìlú di àkójọ àlàpà,
3Nítorí náà àwọn ènìyàn alágbára yóò
4Ìwọ ti jẹ́ ààbò fún àwọn òtòṣì
5àti gẹ́gẹ́ bí ooru ní aginjù.
6Ní orí òkè yìí ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun
7Ní orí òkè yìí ni yóò pa
8Òun yóò sì gbé ikú mì títí láé.
9Ní ọjọ́ náà wọn yóò sọ pé,
10Ọwọ́ Olúwa yóò sinmi lé orí òkè yìí
11Wọn yóò na ọwọ́ wọn jáde nínú rẹ̀,
12Òun yóò sì bi gbogbo ògiri gíga alágbára yín lulẹ̀