1Ọ̀rọ̀-ìmọ̀ tí ó kan aginjù lẹ́bàá Òkun.
2Ìran tí a ń fojú ṣọ́nà fún ni a ti fihàn mí
3Pẹ̀lú èyí, ìrora mu mi lára gírígírí,
4Ọkàn mí dàrú,
5Wọ́n tẹ́ tábìlì,
6Èyí ni ohun tí Olúwa sọ fún mi:
7Nígbà tí ó bá rí àwọn kẹ̀kẹ́ ogun
8Òun sì kígbe pé, kìnnìún kan,
9Wò ó, ọkùnrin kan ni ó ń bọ̀ wá yìí nínú kẹ̀kẹ́ ogun
10Ẹ̀yin ènìyàn mi, tí a gún mọ́lẹ̀ ní ilẹ̀ ìpakà,
11Ọ̀rọ̀-ìmọ̀ tí ó kan Dumahi.
12Alóre náà dáhùn wí pé,
13Ọ̀rọ̀-ìmọ̀ tí ó kan Arabia.
14gbé omi wá fún àwọn tí òǹgbẹ ń gbẹ;
15Wọ́n sá kúrò lọ́wọ́ idà,
16Èyí ni ohun tí Olúwa sọ fún mi: “Láàrín ọdún kan, gẹ́gẹ́ bí ìwọ̀fà tí ó wà lábẹ́ ọgbà, í ti í kà á, gbogbo ògo ìlú Kedari yóò wá sí òpin.
17Àwọn tafàtafà tí ó sálà, àwọn jagunjagun ìlú Kedari kò ní tó nǹkan.” Olúwa, Ọlọ́run Israẹli ni ó ti sọ̀rọ̀.