1Ní ọjọ́ náà ni ìwọ ó wí pé,
2Nítòótọ́ Ọlọ́run ni ìgbàlà mi,
3Pẹ̀lú ayọ̀ ni ìwọ yóò máa pọn omi
4Ní ọjọ́ náà, ìwọ yóò wí pé,
5Kọ orin sí Olúwa, nítorí ó ti ṣe ohun tí ó lógo,
6Kígbe sókè kí o sì kọrin fún ayọ̀, ẹ̀yin ènìyàn Sioni,
Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní · iorubá
1Ní ọjọ́ náà ni ìwọ ó wí pé,
2Nítòótọ́ Ọlọ́run ni ìgbàlà mi,
3Pẹ̀lú ayọ̀ ni ìwọ yóò máa pọn omi
4Ní ọjọ́ náà, ìwọ yóò wí pé,
5Kọ orin sí Olúwa, nítorí ó ti ṣe ohun tí ó lógo,
6Kígbe sókè kí o sì kọrin fún ayọ̀, ẹ̀yin ènìyàn Sioni,