1Ẹ béèrè òjò nígbà àrọ̀kúrò ni ọwọ́ Olúwa;
2Nítorí àwọn òrìṣà tí sọ̀rọ̀ asán,
3“Ìbínú mi ru sí àwọn darandaran,
4Láti ọ̀dọ̀ rẹ̀ ni òkúta igun ilé ti jáde wá,
5Gbogbo wọn yóò sì dàbí ọkùnrin
6“Èmi o sì mú ilé Juda ní agbára,
7Efraimu yóò sì ṣe bí alágbára,
8Èmi ó kọ sí wọn, èmi ó sì ṣà wọ́n jọ;
9Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé mo tú wọn káàkiri orílẹ̀-èdè:
10Èmi ó sì tún mú wọn padà kúrò ni ilẹ̀ Ejibiti pẹ̀lú,
11Wọn yóò sì la Òkun wàhálà já,
12Èmi ó sì mú wọn ní agbára nínú Olúwa;