1Ọlọ́run, èéṣe tí ìwọ fi kọ̀ wá sílẹ̀ títí láé?
2Rántí àwọn ènìyàn tí ìwọ ti rà nígbà àtijọ́,
3Yí ẹsẹ̀ rẹ padà sí ìparun ayérayé wọn,
4Àwọn ọ̀tá rẹ ń bú ramúramù
5Wọ́n ń rí bí ọkùnrin tí ó gbé àáké rẹ̀ sókè
6Ṣùgbọ́n nísinsin yìí, iṣẹ́ ọnà fínfín,
7Wọ́n sun ibi mímọ́ rẹ lulẹ̀
8Wọ́n wí ní ọkàn wọn. “Àwa ó run wọ́n pátápátá!”
9A kò fún wa ní àmì iṣẹ́ ìyanu kankan;
10Àwọn ọ̀tá yóò ti kùn sí ọ pẹ́ tó, Ọlọ́run?
11Èéṣe tí ìwọ fi dá ọwọ́ rẹ dúró, ọwọ́ ọ̀tún rẹ?
12Ṣùgbọ́n ìwọ Ọlọ́run ni ọba mi láti ìgbà pípẹ́;
13Ìwọ ni ó la òkun sílẹ̀ nípa agbára rẹ;
14Ìwọ fọ́ orí Lefitani túútúú, o sì fi ṣe oúnjẹ fun àwọn ẹ̀dá tí ń gbé inú ijù
15Ìwọ ya orísun omi àti ìṣàn omi;
16Tìrẹ ni ọ̀sán, tìrẹ ni òru pẹ̀lú;
17Ìwọ pààlà etí ayé;
18Rántí bí àwọn ọ̀tá ń kẹ́gàn rẹ, Olúwa
19Má ṣe fi ẹ̀mí àdàbà rẹ fún ẹranko igbó búburú;
20Bojú wo májẹ̀mú rẹ,
21Má ṣe jẹ́ kí àwọn aninilára padà sẹ́yìn nínú ìtìjú
22Dìde, Ọlọ́run, gba ẹjọ́ ara rẹ rò;
23Má ṣe gbàgbé ohùn àwọn ọ̀tá rẹ,