1Nínú Ọlọ́run nìkan ni ọkàn mi ti rí ìsinmi;
2Òun nìkan ní àpáta mi àti ìgbàlà mi;
3Ẹ̀yin ó ti máa kọ́lú ènìyàn kan pẹ́ tó?
4Kìkì èrò wọn ni láti bì ṣubú
5Nínú Ọlọ́run nìkan ni ìsinmi wà, ìwọ Ọlọ́run mi.
6Òun nìkan ní àpáta àti ìgbàlà mi;
7Ìgbàlà mi àti ògo mi dúró nínú Ọlọ́run;
8Gbẹ́kẹ̀lé ní gbogbo ìgbà, ẹ̀yin ènìyàn;
9Nítòótọ́, asán ni àwọn ọmọ ènìyàn,
10Má ṣe gbẹ́kẹ̀lé ìnilára,
11Ọlọ́run ti sọ̀rọ̀ lẹ́ẹ̀kejì,
12pẹ̀lúpẹ̀lú, Olúwa, tìrẹ ni àánú;