1Ọlọ́run ni ààbò àti agbára wa
2Nítorí náà àwa kì yóò bẹ̀rù, bí a tilẹ̀ ṣí ayé ní ìdí,
3Tí omi rẹ̀ tilẹ̀ ń hó tí ó sì ń mì
4Odò ńlá kan wà tí ṣíṣàn rẹ̀ mú inú ìlú Ọlọ́run dùn,
5Ọlọ́run wà pẹ̀lú rẹ̀, kò ní yẹ̀:
6Àwọn orílẹ̀-èdè ń bínú, àwọn ilẹ̀ ọba ṣubú,
7Olúwa àwọn ọmọ-ogun wà pẹ̀lú wa,
8Ẹ wá wo iṣẹ́ Olúwa
9O mú ọ̀tẹ̀ tán de òpin ilẹ̀ ayé
10Ẹ dúró jẹ́ẹ́, kí ẹ sì mọ̀ pé èmi ní Ọlọ́run.
11Olúwa àwọn ọmọ-ogun wà pẹ̀lú wa;