1Dá mi lóhùn nígbà tí mo bá pè ọ́,
2Báwo ni yóò ṣe pẹ́ tó, ẹ̀yin ọmọ ènìyàn, tí ẹ ó ṣe sọ ògo mi di ìtìjú?
3Ṣùgbọ́n kí ẹ mọ̀ pé, Olúwa ti ya ẹni olódodo sọ́tọ̀ fún ara rẹ̀;
4Ẹ bínú ẹ má ṣe ṣẹ̀,
5Ẹ rú ẹbọ òdodo
6Ọ̀pọ̀lọpọ̀ ló ń béèrè pé, “Ta ni yóò ṣe rere fún wa?”
7Ìwọ ti fi ayọ̀ púpọ̀ kún ọkàn mi
8Èmi yóò dùbúlẹ̀, èmi ó sì sùn ní àlàáfíà,