We Believe JesusFé, Esperança e Nova Vida

Saamu 22

Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní · iorubá

← Saamu 21 Saamu Saamu 23 →

1Ọlọ́run mi, Ọlọ́run mi, èéṣe tí ìwọ fi kọ̀ mí sílẹ̀?

2Ọlọ́run mi, ní ọ̀sán gangan ni mo kígbe, ṣùgbọ́n ìwọ kò dá mi ní ohùn:

3Ṣùgbọ́n síbẹ̀ ẹni mímọ́ ni Ìwọ;

4Àwọn baba ńlá wa ní ìgbẹ́kẹ̀lé nínú rẹ;

5Ìwọ ni wọ́n sun ẹkún sí, wọ́n sì ní ìgbàlà;

6Ṣùgbọ́n kòkòrò ní mo jẹ́, kì í sì í ṣe ènìyàn;

7Gbogbo àwọn tí ó rí mí fi mí ṣe ẹlẹ́yà;

8“Ó gbẹ́kẹ̀ rẹ̀ lé Olúwa;

9Síbẹ̀ ìwọ ni ó ti mú mi wá láti inú;

10Ìwọ ni a fi mí lé lọ́wọ́ láti inú ìyá mi wá,

11Má ṣe jìnnà sí mi,

12Ọ̀pọ̀ akọ màlúù yí mi ká;

13Wọ́n ya ẹnu wọn sì mi bí i kìnnìún tí ń dọdẹ kiri,

14A dà mí jáde gẹ́gẹ́ bí omi,

15Agbára mí ti gbẹ bí àpáàdì,

16Àwọn ajá yí mi ká;

17Mo lè ka gbogbo àwọn egungun mi;

18Wọ́n pín aṣọ mi láàrín ara wọn

19Ṣùgbọ́n ìwọ, Olúwa, má ṣe jìnnà sí mi.

20Gba ọkàn mi sílẹ̀ lọ́wọ́ idà,

21Gba ọkàn mi sílẹ̀ lọ́wọ́ kìnnìún;

22Èmi yóò kéde orúkọ rẹ láàrín arákùnrin àti arábìnrin mi;

23Ẹ̀yin tí ẹ bẹ̀rù Olúwa, ẹ yìn ín!

24Nítorí pé òun kò ṣátá, bẹ́ẹ̀ ni kò sì kórìíra

25Láti ọ̀dọ̀ rẹ̀ ni ìyìn mi yóò ti wá nínú àjọ ńlá;

26tálákà yóò jẹ yóò sì yó;

27Gbogbo òpin ayé ni yóò rántí

28nítorí ìjọba ni ti Olúwa.

29Bẹ́ẹ̀ náà ni gbogbo àwọn olówó ayé wọn yóò ṣe àsè, wọn yóò sì sìn;

30Irú-ọmọ rẹ̀ yóò sìn ín;

31Wọn yóò polongo òdodo rẹ̀

← Saamu 21 Saamu Saamu 23 →

Saamu 22 — iorubá:

Biblica® Open Nkanda wu Moyo, Nguizani Yimona ayi Minkunga 2002