1Kí Olúwa kí ó gbóhùn rẹ ní ọjọ́ ìpọ́njú;
2Kí ó rán ìrànlọ́wọ́ sí ọ, láti ibi mímọ́
3Kí ó sì rántí gbogbo ẹbọ rẹ
4Kí ó fi fún ọ gẹ́gẹ́ bi ti èrò ọkàn rẹ
5Àwa yóò hó fún ayọ̀ nígbà tí o bá di aṣẹ́gun
6Nísinsin yìí, èmi mọ̀ wí pé,
7Àwọn mìíràn gbẹ́kẹ̀ wọn lé kẹ̀kẹ́, àwọn mìíràn gbẹ́kẹ̀ wọn lé ẹṣin,
8Wọ́n wólẹ̀, ní eékún, wọ́n sì ṣubú,
9Olúwa, fi ìṣẹ́gun fún ọba!