1Pa mí mọ́, Ọlọ́run,
2Mo sọ fún Olúwa, “Ìwọ ni Olúwa mi,
3Sí àwọn ènìyàn tí ó wà ní ayé,
4Ìṣòro àwọn wọ̀n-ọn-nì yóò pọ̀ sí i, àní àwọn tí ń tọ ọlọ́run mìíràn lẹ́yìn.
5Olúwa, ni ìpín ìní mi tí mo yàn àti ago mi,
6Okùn ààlà ilẹ̀ ti bọ́ sí ọ̀dọ̀ mi ní ibi dídára;
7Èmi yóò yin Olúwa, ẹni tí ó gbà mí ní ìyànjú;
8Mo ti gbé Olúwa síwájú mi ní ìgbà gbogbo.
9Nítorí èyí, ọkàn mi yọ̀, ahọ́n mi pẹ̀lú ń fò fáyọ̀;
10nítorí ìwọ kò ní fi ọ̀kan sílẹ̀ nínú isà òkú,
11Ìwọ ti fi ipa ọ̀nà ìyè hàn mí;