1Ẹ fi ìyìn fún Olúwa.
2Olúwa kọ́ Jerusalẹmu;
3Ó wo àwọn tí ọkàn wọ́n bàjẹ́ sàn
4Ó ka iye àwọn ìràwọ̀
5Títóbi ni Olúwa wa ó sì pọ̀ ní agbára
6Olúwa wa pẹ̀lú àwọn onírẹ̀lẹ̀
7Fi ọpẹ́ kọrin sí Olúwa
8Ó fi ìkùùkuu bo àwọ̀ sánmọ̀
9Ó pèsè oúnjẹ fún àwọn ẹranko
10Òun kò ní inú dídùn nínú agbára ẹṣin,
11Olúwa ni ayọ̀ nínú àwọn tí ó bẹ̀rù rẹ̀,
12Yin Olúwa, ìwọ Jerusalẹmu;
13Nítorí tí ó ti mú ọ̀pá ìdábùú ibodè rẹ̀ lágbára,
14Òun jẹ́ kí àlàáfíà wà ní àwọn ẹnu ibodè rẹ̀,
15Òun sì rán àṣẹ rẹ̀ sí ayé
16Ó fi yìnyín fún ni bi irun àgùntàn
17Ó rọ òjò yìnyín rẹ̀ bí òkúta wẹ́wẹ́
18Ó rán ọ̀rọ̀ rẹ̀ jáde ó sì mú wọn yọ̀
19Ó sọ ọ̀rọ̀ rẹ̀ di mí mọ̀ fún Jakọbu
20Òun kó tí ṣe irú èyí sí orílẹ̀-èdè kan rí, bí ó ṣe ti ìdájọ́ rẹ̀