1Olúwa, èmi ké pè ọ́; yára wá sí ọ̀dọ̀ mi.
2Jẹ́ kí àdúrà mi ó wá sí iwájú rẹ bí ẹbọ tùràrí
3Fi ẹ̀ṣọ́ ṣọ́ ẹnu mi, Olúwa:
4Má ṣe jẹ́ kí ọkàn mi fà sí ohun tí ń ṣe ibi,
5Jẹ́ kí olódodo lù mí, ìṣeun ni ó jẹ́:
6A ó ju àwọn alákòóso sílẹ̀ láti bẹ̀bẹ̀ òkúta,
7Wọn yóò wí pé, “Bí ẹni tí ó la aporo sórí ilẹ̀,
8Ṣùgbọ́n ojú mi ń bẹ lára rẹ, Olúwa Olódùmarè;
9Pa mí mọ́ kúrò nínú okùn tí wọn ti dẹ sílẹ̀ fún mi,
10Jẹ́ kí àwọn ẹni búburú ṣubú sínú àwọ̀n ara wọn,