1Aṣiwèrè wí nínú ọkàn rẹ̀ pé,
2Olúwa sì bojú wolẹ̀ láti ọ̀run wá
3Gbogbo wọn sì ti yípadà, gbogbo wọn sì ti díbàjẹ́;
4Ǹjẹ́ olùṣe búburú kò ha ní ìmọ̀?
5Wọ́n wà níbẹ̀, tí a bò mọ́lẹ̀ pẹ̀lú ẹ̀rù,
6Ẹ̀yin olùṣe búburú da èrò àwọn tálákà rú,
7Ìgbàlà àwọn Israẹli yóò ti Sioni wá!