1Bí kò ṣe pé Olúwa bá kọ́ ilé náà
2Asán ni fún ẹ̀yin ti ẹ dìde ní kùtùkùtù
3Kíyèsi i, àwọn ọmọ ni ìní Olúwa:
4Bí ọfà ti rí ní ọwọ́ alágbára,
5Ìbùkún ni fún ọkùnrin náà tí apó rẹ̀ kún fún wọn;
Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní · iorubá
1Bí kò ṣe pé Olúwa bá kọ́ ilé náà
2Asán ni fún ẹ̀yin ti ẹ dìde ní kùtùkùtù
3Kíyèsi i, àwọn ọmọ ni ìní Olúwa:
4Bí ọfà ti rí ní ọwọ́ alágbára,
5Ìbùkún ni fún ọkùnrin náà tí apó rẹ̀ kún fún wọn;