1Ràn wá lọ́wọ́, Olúwa, nítorí ẹni ìwà-bí-Ọlọ́run kò sí mọ́;
2Olúkúlùkù ń parọ́ fún aládùúgbò rẹ̀;
3Kí Olúwa kí ó gé ètè èké wọn
4tí ó wí pé,
5“Nítorí ìnilára àwọn aláìlágbára àti ìkérora àwọn aláìní,
6Ọ̀rọ̀ Olúwa sì jẹ aláìlábùkù,
7Olúwa, ìwọ yóò pa wá mọ́
8Àwọn ènìyàn búburú ń rin ìrìn fáàrí kiri