1Ẹ fi ọpẹ́ fún Olúwa, nítorí tí ó dára;
2Jẹ́ kí Israẹli wí pé:
3Jẹ́ kí ilé Aaroni wí pé:
4Jẹ́ kí àwọn tí ó bẹ̀rù Olúwa wí pé:
5Nínú ìrora mi, mo sọkún sí Olúwa,
6Olúwa ń bẹ fún èmi; èmi kì yóò bẹ̀rù.
7Olúwa ń bẹ fún mi; òun ni olùrànlọ́wọ́ mi.
8Ó dára láti máa gbẹ́kẹ̀lé Olúwa
9Ó dára láti máa gbẹ́kẹ̀lé Olúwa
10Gbogbo àwọn orílẹ̀-èdè yí mi káàkiri,
11Wọ́n yí mi káàkiri ní gbogbo ẹ̀gbẹ́,
12Wọ́n gbá yìn ìn yí mi ká bí oyin,
13Ìwọ tì mí gidigidi kí n lè ṣubú,
14Olúwa ni agbára àti orin mi;
15Ohùn ayọ̀ àti ìgbàlà ń bẹ nínú àgọ́ àwọn olódodo:
16Ọwọ́ ọ̀tún Olúwa ní a gbéga;
17Èmi kì yóò kú, ṣùgbọ́n èmi yóò yè,
18Olúwa bá mi wí gidigidi,
19Ṣí ìlẹ̀kùn ẹnu-ọ̀nà òdodo fún mi:
20Èyí ni ìlẹ̀kùn Olúwa
21Èmi yóò fi ọpẹ́ fún ọ, nítorí ó dá mi lóhùn;
22Òkúta tí àwọn ọ̀mọ̀lé kọ̀sílẹ̀,
23Olúwa ti ṣe èyí,
24Èyí ni ọjọ́ tí Olúwa dá:
25Olúwa, gbà wá;
26Ìbùkún ni ẹni tí ń bọ̀ wá ní orúkọ Olúwa.
27Olúwa ni Ọlọ́run,
28Ìwọ ni Ọlọ́run mi, èmi yóò máa fi ọpẹ́ fún ọ;
29Ẹ fi ọpẹ́ fún Olúwa, nítorí tí ó ṣeun;