1Ìbùkún ni fún ọkùnrin náà,
2Ṣùgbọ́n ayọ̀ inú rẹ̀ wà nínú òfin Olúwa
3Ó dàbí igi tí a gbìn sí etí odò tí ń sàn,
4Kò le rí bẹ́ẹ̀ fún àwọn ènìyàn búburú!
5Nítorí náà àwọn ènìyàn búburú kì yóò le è dìde dúró ní ìdájọ́,
6Nítorí Olúwa ń ṣọ́ ọ̀nà àwọn olódodo,