1Ègbé ni fún ìlú aninilára,
2Òun kò gbọ́rọ̀ sí ẹnikẹ́ni,
3Àwọn olórí rẹ̀ jẹ́ kìnnìún tí ń ké ramúramù,
4Àwọn wòlíì rẹ̀ gbéraga,
5Olúwa ni àárín rẹ̀ jẹ́ olódodo;
6“Èmi ti ké àwọn orílẹ̀-èdè kúrò,
7Èmi wí fún ìlú náà wí pé,
8Nítorí náà ẹ dúró dè mí,” ni Olúwa wí,
9“Nígbà náà ni èmi yóò yí èdè àwọn ènìyàn padà sí èdè mímọ́,
10Láti òkè odò Etiopia,
11Ní ọjọ́ náà ni a kì yóò sì dójútì
12Ṣùgbọ́n Èmi yóò fi àwọn ọlọ́kàn tútù
13Àwọn ìyókù Israẹli kì yóò hùwà ibi,
14Kọrin, ìwọ ọmọbìnrin Sioni,
15Olúwa ti mú ìdájọ́ rẹ wọ̀n-ọn-nì kúrò,
16Ní ọjọ́ náà, wọn yóò sọ fún Jerusalẹmu pé,
17Olúwa Ọlọ́run rẹ wà pẹ̀lú rẹ,
18“Èmi ó kó àwọn tí ó ń banújẹ́ fún àjọ̀dún tí a yàn jọ,
19Ní àkókò náà
20Ní àkókò náà ni èmi yóò ṣà yín jọ;