1Wọ̀nyí ni àwọn òwe mìíràn tí Solomoni pa, tí àwọn ọkùnrin Hesekiah ọba Juda dà kọ.
2Ògo Ọlọ́run ní láti fi ọ̀rọ̀ kan pamọ́;
3Bí ọ̀run ṣe ga tó tí ayé sì jì
4Mú ìdàrọ́ kúrò lára fàdákà
5Mú ènìyàn búburú kúrò níwájú ọba
6Má ṣe gbé ara rẹ ga níwájú ọba,
7ó sàn kí ó wí fún ọ pé, “Gòkè wá síyìn-ín,”
8Ohun tí o ti fi ojú ara rẹ rí
9Bí o bá ń ṣe àwíjàre rẹ níwájú aládùúgbò rẹ,
10àìṣe bẹ́ẹ̀ ẹni tí ó gbọ́ ọ le dójútì ọ́
11Ọ̀rọ̀ tí a sọ ní àkókò tí ó yẹ
12Bí i yẹtí wúrà tàbí ohun ọ̀ṣọ́ ti wúrà dáradára
13Bí títutù òjò yìnyín ní àsìkò ìkórè
14Bí ojú ṣíṣú àti afẹ́fẹ́ láìsí òjò
15Nípa sùúrù a lè yí ọba lọ́kàn padà
16Bí ìwọ bá rí oyin, jẹ ẹ́ ní ìwọ̀nba
17Má ṣe máa lọ sí ilé aládùúgbò rẹ nígbà gbogbo
18Bí ọ̀pá, idà tàbí ọ̀kọ̀ tí ó mú
19Bí eyín tí ó bàjẹ́ tàbí ẹsẹ̀ tí ó rọ
20Bí ẹni tí ó bọ́ra kalẹ̀ ní ọjọ́ tí òtútù mú,
21Bí ebi bá ń pa ọ̀tá rẹ, fún un ní oúnjẹ jẹ;
22Nípa ṣíṣe báyìí, ìwọ yóò wa ẹ̀yín iná lé e lórí
23Bí afẹ́fẹ́ gúúsù ti í mú òjò wá,
24Ó sàn láti gbé ní ibi igun kan lórí òrùlé
25Bí omi tútù sí ọkàn tí ń ṣe àárẹ̀
26Bí ìsun tí ó di àbàtà tàbí kànga tí omi rẹ̀ bàjẹ́
27Kò dára láti jẹ oyin àjẹjù,
28Bí ìlú tí odi rẹ̀ ti wó lulẹ̀