1Ẹ fi etí sí ohun tí Olúwa wí:
2“Gbọ́, ìwọ òkè ńlá, ẹ̀sùn Olúwa;
3“Ẹ̀yin ènìyàn mi, kí ni mo ṣe fún yín?
4Nítorí èmi mú un yín gòkè láti ilẹ̀ Ejibiti wá,
5Ìwọ ènìyàn mi,
6Kí ni èmi yóò ha mú wá síwájú Olúwa
7Ǹjẹ́ Olúwa yóò ní inú dídùn sí ẹgbẹgbàarùn-ún àgbò,
8Ó ti fihàn ọ́, ìwọ ènìyàn, ohun tí ó dára,
9Gbọ́! Ohùn Olúwa kígbe sí ìlú ńlá náà,
10Ǹjẹ́ ìṣúra ìwà búburú ha wà
11Ǹjẹ́ èmi ha lè kà wọ́n sí mímọ́
12Àwọn ọlọ́rọ̀ inú rẹ̀ kún fún ìwà ipá;
13Nítorí náà ni èmi yóò ṣe mú ọ ṣàìsàn ní lílù ọ́,
14Ìwọ yóò jẹun ṣùgbọ́n kì yóò yó;
15Ìwọ yóò gbìn ṣùgbọ́n ìwọ kì yóò kórè
16Nítorí tí ìwọ ti pa òfin Omri mọ́,