1Báwo ni ìlú ṣe jókòó nìkan,
2Ọ̀gànjọ́ òru ni ó fi máa ń sọkún kíkorò
3Lẹ́yìn ìjìyà àti ìpọ́njú nínú oko ẹrú,
4Gbogbo ọ̀nà tí ó wọ Sioni ń ṣọ̀fọ̀,
5Àwọn aninilára rẹ̀ gbogbo di olúwa rẹ̀,
6Gbogbo ẹwà ti di ohun ìgbàgbé
7Ní ọjọ́ ìpọ́njú àti àrìnká rẹ̀ ni
8Jerusalẹmu sì ti dẹ́ṣẹ̀ púpọ̀
9Ìdọ̀tí wà ní etí aṣọ rẹ̀,
10Ọ̀tá ti gbọ́wọ́ lé
11Àwọn ènìyàn rẹ̀ ń kérora
12“Kò ha jẹ́ nǹkan kan sí i yín?
13“Ó rán iná láti òkè
14“Ẹ̀ṣẹ̀ mi ti di sísopọ̀ sí àjàgà;
15“Olúwa kọ
16“Ìdí nìyí tí mo fi ń sọkún
17Sioni na ọwọ́ jáde,
18“Olóòtítọ́ ni Olúwa,
19“Mo pe àwọn ọ̀rẹ́ mi
20“Olúwa, wò ó, bí mo ti wà nínú ìnira!
21“Àwọn ènìyàn ti gbọ́ ìrora mi,
22“Jẹ́ kí ìwà ìkà wọn wá síwájú rẹ;