We Believe JesusFé, Esperança e Nova Vida

Jobu 6

Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní · iorubá

← Jobu 5 Jobu Jobu 7 →

1Jobu sì dáhùn ó si wí pé,

2“Háà! À bá lè wọ́n ìbìnújẹ́ mi nínú òsùwọ̀n,

3Ǹjẹ́ nísinsin yìí, ìbá wúwo jú iyanrìn òkun lọ,

4Nítorí pé ọfà Olódùmarè wọ̀ mi nínú,

5Ǹjẹ́ kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ igbó á máa dún nígbà tí ó bá ní koríko,

6A ha lè jẹ ohun tí kò ní adùn ní àìní iyọ̀,

7Ohun ti ọ̀kan mi kọ̀ láti tọ́wò,

8“Háà! èmi ìbá lè rí ìbéèrè mi gbà;

9Àní Ọlọ́run ìbá jẹ́ pa mí run,

10Nígbà náà ní èmi ìbá ní ìtùnú síbẹ̀,

11“Kí ní agbára mi tí èmi ó fi retí?

12Agbára mi ha ṣe agbára òkúta bí?

13Ìrànlọ́wọ́ mi kò ha wà nínú mi:

14“Ẹni tí àyà rẹ̀ yọ́ dànù, ta ni a bá máa ṣàánú fún láti ọ̀dọ̀ ọ̀rẹ́ rẹ̀ wá,

15Àwọn ará mi dàbí odò tí kò ṣe gbẹ́kẹ̀lé

16Tí ó dúdú nítorí omi dídì,

17Nígbàkígbà tí wọ́n bá gbóná wọn a sì yọ́ sàn lọ,

18Àwọn oníṣòwò yà kúrò ní ọ̀nà wọn,

19Ẹgbẹ́ oníṣòwò Tema ń wá omi,

20Wọ́n káàárẹ̀, nítorí tí wọ́n gbẹ́kẹ̀ wọn lé e;

21Ǹjẹ́ nísinsin yìí, ẹ̀yin dàbí wọn;

22Èmi ó ha wí pé, ‘Ẹ mú ohun fún mi wá,

23Tàbí, ẹ gbà mí lọ́wọ́ ọ̀tá ni,

24“Ẹ kọ́ mi, èmi ó sì pa ẹnu mi mọ́

25Wò ó! Bí ọ̀rọ̀ òtítọ́ ti lágbára tó

26Ẹ̀yin ṣè bí ẹ tún ọ̀rọ̀ mi ṣe

27Àní ẹ̀yin ṣe gẹ́gẹ́ bí aláìní baba,

28“Nítorí náà, kí èyí kí ó tó fún yín.

29Èmi ń bẹ̀ yín, ẹ padà, kí ó má sì ṣe jásí ẹ̀ṣẹ̀;

30Àìṣedéédéé ha wà ní ahọ́n mi?

← Jobu 5 Jobu Jobu 7 →

Jobu 6 — iorubá:

Biblica® Open Nkanda wu Moyo, Nguizani Yimona ayi Minkunga 2002