1Elihu sì wí pe:
2“Ìwọ rò pé èyí ha tọ́, tí ìwọ wí pé,
3Nítorí tí ìwọ wí pé èrè kí ní yóò jásí fún ọ,
4“Èmi ó dá ọ lóhùn
5Síjú wo ọ̀run; kí o rí i, kí ó sì
6Bí ìwọ bá dẹ́ṣẹ̀, kí ni ìwọ fi sẹ̀ sí?
7Bí ìwọ bá sì ṣe olódodo, kí ni ìwọ fi fún un,
8Ìwà búburú rẹ ni fún ènìyàn bí ìwọ;
9“Nípa ọ̀pọ̀lọpọ̀ ìninilára, wọ́n mú ni kígbe;
10Ṣùgbọ́n kò sí ẹni tí ó wí pé,
11tí òun kọ́ wa ní ẹ̀kọ́ jù àwọn ẹranko ayé lọ,
12Nígbà náà ni wọ́n ń ké ṣùgbọ́n Ọlọ́run kò dáhùn
13Nítòótọ́ Ọlọ́run kì yóò gbọ́ ọ̀rọ̀ asán;
14Bí ó tilẹ̀ ṣe pé ìwọ wí pé ìwọ kì í rí i,
15Ṣùgbọ́n nísinsin yìí nítorí tí ìbínú rẹ̀ kò tí fìyà jẹ ni,
16Nítorí náà ní Jobu ṣe ya ẹnu rẹ̀