1“Ènìyàn tí a bí nínú obìnrin,
2Ó jáde wá bí ìtànná ewéko, a sì ké e lulẹ̀;
3Ìwọ sì ń síjú rẹ wò irú èyí ni?
4Ta ni ó lè mú ohun mímọ́ láti inú àìmọ́ jáde wá?
5Ǹjẹ́ a ti pinnu ọjọ́ rẹ̀,
6Yípadà kúrò lọ́dọ̀ rẹ̀, kí ó lè sinmi,
7“Nítorí pé ìrètí wà fún igi, bí a bá
8Bí gbòǹgbò rẹ̀ tilẹ̀ di ogbó nínú ilẹ̀,
9síbẹ̀ nígbà tí ó bá gbóòórùn omi,
10Ṣùgbọ́n ènìyàn kú, a sì dàánù,
11“Bí omi ti í tán nínú ipa odò,
12bẹ́ẹ̀ ni ènìyàn dùbúlẹ̀ tí kò sì dìde mọ́;
13“Háà! ìwọ ìbá fi mí pamọ́ ní ipò òkú,
14Bí ènìyàn bá kú yóò sì tún yè bí?
15Ìwọ ìbá pè, èmi ìbá sì dá ọ lóhùn;
16Ṣùgbọ́n nísinsin yìí ìwọ ń kaye ìṣísẹ̀ mi;
17A fi èdìdì di ìrékọjá mi sínú àpò,
18“Àti nítòótọ́ òkè ńlá tí ó ṣubú, ó dasán,
19Omi a máa yinrin òkúta, ìwọ a sì
20Ìwọ ṣẹ́gun rẹ̀ láéláé, òun sì kọjá lọ!
21Àwọn ọmọ rẹ̀ bọ́ sí ipò ọlá, òun kò sì mọ̀;
22Ṣùgbọ́n ẹran-ara rẹ̀ ni yóò rí ìrora