1“Ẹ̀yin ènìyàn Benjamini, sá sí ibi ààbò!
2Èmi yóò pa ọmọbìnrin Sioni run,
3Olùṣọ́-àgùntàn pẹ̀lú agbo wọn yóò gbóguntì wọ́n.
4“Ẹ ya ará yín sí mímọ́ láti bá a jagun!
5Nítorí náà, ẹ dìde, ẹ jẹ́ kí a kọlù ú ní àṣálẹ́
6Èyí ni ohun tí Olúwa Ọlọ́run Àwọn ọmọ-ogun wí:
7Gẹ́gẹ́ bí kànga ṣe ń da omi inú rẹ̀ sílẹ̀,
8Ìwọ Jerusalẹmu, gba ìkìlọ̀,
9Èyí ni ohun tí Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí:
10Ta ni ẹni tí mo lè bá sọ̀rọ̀ àti tí mo lè fún ní ìmọ̀ràn?
11Èmi kún fún ìbínú Olúwa,
12Ilé wọn o sì di ti ẹlòmíràn,
13“Láti orí ẹni tí ó kéré sí orí ẹni tí ó tóbi ju,
14Wọ́n sì ń wo ọgbẹ́ àwọn ènìyàn
15Ojú ha a tì wọ́n nítorí ìwà ìríra wọn bí?
16Èyí ni ohun tí Olúwa wí:
17Èmi yan olùṣọ́ fún un yín,
18Nítorí náà, gbọ́ ẹ̀yin orílẹ̀-èdè;
19Gbọ́, ìwọ ayé!
20Èrè wo ni ó wà fún mi nínú tùràrí láti Ṣeba wá,
21Nítorí náà, èyí ni ohun tí Olúwa wí:
22Báyìí ni Olúwa wí:
23Wọ́n sì dìmọ́ra pẹ̀lú ọrun àti ọ̀kọ̀,
24Àwa ti gbọ́ ìròyìn nípa wọn,
25Má ṣe jáde lọ sí orí pápá
26Ẹ̀yin ènìyàn mi, ẹ gbé aṣọ ọ̀fọ̀ wọ̀,
27“Èmi ti fi ẹ́ ṣe ẹni tí yóò máa yọ́
28Ọlọ́tẹ̀ tí ọkàn rẹ̀ le ní gbogbo wọn.
29Ewìrì a fẹ́ná kíkankíkan,
30A pè wọ́n ní fàdákà tí a kọ̀sílẹ̀,