We Believe JesusFé, Esperança e Nova Vida

Jeremiah 6

Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní · iorubá

← Jeremiah 5 Jeremiah Jeremiah 7 →

1“Ẹ̀yin ènìyàn Benjamini, sá sí ibi ààbò!

2Èmi yóò pa ọmọbìnrin Sioni run,

3Olùṣọ́-àgùntàn pẹ̀lú agbo wọn yóò gbóguntì wọ́n.

4“Ẹ ya ará yín sí mímọ́ láti bá a jagun!

5Nítorí náà, ẹ dìde, ẹ jẹ́ kí a kọlù ú ní àṣálẹ́

6Èyí ni ohun tí Olúwa Ọlọ́run Àwọn ọmọ-ogun wí:

7Gẹ́gẹ́ bí kànga ṣe ń da omi inú rẹ̀ sílẹ̀,

8Ìwọ Jerusalẹmu, gba ìkìlọ̀,

9Èyí ni ohun tí Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí:

10Ta ni ẹni tí mo lè bá sọ̀rọ̀ àti tí mo lè fún ní ìmọ̀ràn?

11Èmi kún fún ìbínú Olúwa,

12Ilé wọn o sì di ti ẹlòmíràn,

13“Láti orí ẹni tí ó kéré sí orí ẹni tí ó tóbi ju,

14Wọ́n sì ń wo ọgbẹ́ àwọn ènìyàn

15Ojú ha a tì wọ́n nítorí ìwà ìríra wọn bí?

16Èyí ni ohun tí Olúwa wí:

17Èmi yan olùṣọ́ fún un yín,

18Nítorí náà, gbọ́ ẹ̀yin orílẹ̀-èdè;

19Gbọ́, ìwọ ayé!

20Èrè wo ni ó wà fún mi nínú tùràrí láti Ṣeba wá,

21Nítorí náà, èyí ni ohun tí Olúwa wí:

22Báyìí ni Olúwa wí:

23Wọ́n sì dìmọ́ra pẹ̀lú ọrun àti ọ̀kọ̀,

24Àwa ti gbọ́ ìròyìn nípa wọn,

25Má ṣe jáde lọ sí orí pápá

26Ẹ̀yin ènìyàn mi, ẹ gbé aṣọ ọ̀fọ̀ wọ̀,

27“Èmi ti fi ẹ́ ṣe ẹni tí yóò máa yọ́

28Ọlọ́tẹ̀ tí ọkàn rẹ̀ le ní gbogbo wọn.

29Ewìrì a fẹ́ná kíkankíkan,

30A pè wọ́n ní fàdákà tí a kọ̀sílẹ̀,

← Jeremiah 5 Jeremiah Jeremiah 7 →

Jeremiah 6 — iorubá:

Biblica® Open Nkanda wu Moyo, Nguizani Yimona ayi Minkunga 2002