1Ọ̀rọ̀ tí ó tọ Jeremiah wá láti ọ̀dọ̀ Olúwa wá, wí pé:
2“Báyìí ni Olúwa Ọlọ́run Israẹli wí, pé: ‘Ìwọ kọ gbogbo ọ̀rọ̀ tí mo ti bá ọ sọ sínú ìwé kan.
3Ọjọ́ ń bọ̀ nígbà tí ń ó mú àwọn ènìyàn mi, àwọn ọmọ Israẹli àti Juda kúrò nínú ìgbèkùn, tí n ó sì dá wọn padà sí orí ilẹ̀ tí mo fi fún àwọn baba ńlá wọn láti ní,’ ni Olúwa Ọlọ́run wí.”
4Ìwọ̀nyí ni àwọn ọ̀rọ̀ Olúwa Ọlọ́run sí Israẹli àti Juda:
5“Èyí ni ohun tí Olúwa wí:
6Béèrè kí o sì rí.
7Ọjọ́ náà yóò ha ti burú tó!
8“ ‘Ní ọjọ́ náà,’ Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí pé,
9Dípò bẹ́ẹ̀ wọn yóò máa sin Olúwa Ọlọ́run wọn
10“ ‘Nítorí náà, má ṣe bẹ̀rù, ìwọ Jakọbu ìránṣẹ́ mi,
11Èmi wà pẹ̀lú rẹ, n ó sì gbà ọ́,’
12“Èyí ni ohun tí Olúwa wí:
13Kò sí ẹnìkan tí yóò bẹ̀bẹ̀ fún àìṣedéédéé yín,
14Gbogbo àwọn olùfẹ́ rẹ ti gbàgbé rẹ,
15Èéṣe tí ẹ̀yin fi ń kígbe nítorí ọgbẹ́ yín,
16“ ‘Ṣùgbọ́n ẹni tí ó bá ṣe yín ní ibi ni ibi yóò bá,
17Ṣùgbọ́n èmi yóò fi ẹ̀kúnrẹ́rẹ́ ìlera fún yín,
18“Èyí ni ohun tí Olúwa wí:
19Láti ẹnu wọn ni orin ọpẹ́ àti
20Ọmọ ọmọ wọn yóò wà bí i ti ìgbàanì
21Ọ̀kan nínú wọn ni yóò jẹ́ olórí wọn,
22‘Nítorí náà, ẹ̀yin yóò jẹ́ ènìyàn mi,
23Wò ó, ìbínú Olúwa yóò tú jáde,
24Ìbínú ńlá Olúwa kò ní dẹ̀yìn lẹ́yìn