1Ọ̀rọ̀ Olúwa sì tọ̀ mí wá wí pé:
2“Lọ kí o sì kéde sí etí Jerusalẹmu pé:
3Israẹli jẹ́ mímọ́ sí Olúwa,
4Gbọ́ ọ̀rọ̀ Olúwa, ẹ̀yin ìdílé Jakọbu
5Báyìí ni Olúwa wí:
6Wọn kò béèrè, ‘Níbo ni Olúwa wà,
7Èmi mú yín wá sí ilẹ̀ ọlọ́ràá
8Àwọn àlùfáà kò béèrè wí pé,
9“Nítorí náà, mo fi ẹ̀sùn kàn yín lẹ́ẹ̀kan sí i,”
10Rékọjá lọ sí erékùṣù àwọn ara Kittimu, kí ẹ sì wò ó,
11Orílẹ̀-èdè kan ha á pa ọlọ́run rẹ̀ dà?
12Àwọn ènìyàn mi ti dẹ́ṣẹ̀ méjì
13“Àwọn ènìyàn mi ti dẹ́ṣẹ̀ méjì,
14Israẹli ha á jẹ́ ọmọ ọ̀dọ̀ ẹrú nípa ìbí?
15Àwọn kìnnìún ké ramúramù;
16Bákan náà, àwọn ọkùnrin Memfisi àti Tafanesi
17Ẹ̀yin kò ha a ti fa èyí sórí ara yín
18Kí ló dé tí o ṣe wá lọ Ejibiti
19Iṣẹ́ búburú yín yóò fìyà jẹ yín
20“Nígbà àtijọ́, o ti fọ́ àjàgà rẹ sọnù,
21Èmi ti gbìn ọ́ gẹ́gẹ́ bí àjàrà ọ̀tọ̀,
22Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé o wẹ ara rẹ pẹ̀lú sódà
23“Báwo ni ìwọ ṣe wí pé, ‘Èmi kò ṣe aláìmọ́,
24Kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ igbó tí ń gbé aginjù
25Dá ẹsẹ̀ dúró láìwọ bàtà,
26“Gẹ́gẹ́ bí a ṣe ń dójútì olè nígbà tí a bá mú u,
27Wọ́n sọ fún igi pé, ‘Ìwọ ni baba mi,’
28Níbo wá ni àwọn ọlọ́run tí ẹ ṣe fúnra yín ha a wà?
29“Kí ló dé tí o ṣe wá ń fi ẹ̀sùn kàn mí?
30“Nínú asán mo fìyà jẹ àwọn ènìyàn yín,
31“Ẹ̀yin ìran yìí, ẹ kíyèsi ọ̀rọ̀ Olúwa:
32Wúńdíá ha le gbàgbé ohun ọ̀ṣọ́ rẹ̀,
33Ìwọ ti jẹ́ ọlọ́gbọ́n tó nípa ọ̀rọ̀ ìfẹ́!
34Lórí aṣọ rẹ ni wọ́n bá
35ìwọ sọ wí pé, ‘Èmi jẹ́ aláìṣẹ̀;
36Èéṣe tí ìwọ fi ń lọ káàkiri
37Ìwọ yóò sì fi ibẹ̀ sílẹ̀