1Nígbà náà ni Jona gbàdúrà sí Olúwa Ọlọ́run rẹ̀ láti inú ẹja náà wá,
2Ó sì wí pé:
3Nítorí tí ìwọ ti sọ mí sínú ibú,
4Nígbà náà ni mo wí pé,
5Omi yí mi káàkiri, àní títí dé ọkàn;
6Èmi sọ̀kalẹ̀ lọ sí ìsàlẹ̀ àwọn òkè ńlá;
7“Nígbà tí ó rẹ ọkàn mi nínú mi,
8“Àwọn tí ń fàmọ́ òrìṣà èké
9Ṣùgbọ́n èmi yóò fi orin ọpẹ́, rú ẹbọ sí ọ.
10Olúwa sì pàṣẹ fún ẹja náà, ó sì pọ Jona sí orí ilẹ̀ gbígbẹ.