1“Èmi fi ara mi hàn fún àwọn tí kò béèrè fún mi;
2Gbogbo ọjọ́ ni mo ti nawọ́ mi síta
3àwọn ènìyàn tí wọ́n bí mi nínú nígbà gbogbo
4wọ́n ń jókòó láàrín ibojì
5tí ó wí pé, ‘Ẹ sún mẹ́yìn; ẹ má wá sọ́dọ̀ mi,
6“Kíyèsi i, a ti kọ ọ́ síwájú mi,
7àwọn ẹ̀ṣẹ̀ yín àti tàwọn baba yín,”
8Báyìí ni Olúwa wí:
9Èmi yóò mú ìrandíran wá láti ìdílé Jakọbu,
10Ṣaroni yóò di pápá oko fún ọ̀wọ́ ẹran,
11“Ṣùgbọ́n fún ẹ̀yin tí ó kọ Olúwa sílẹ̀
12Èmi yóò yà ọ́ sọ́tọ̀ fún idà,
13Nítorí náà, báyìí ni Olúwa Olódùmarè wí:
14Àwọn ìránṣẹ́ mi yóò kọrin
15Ẹ̀yin yóò fi orúkọ yín sílẹ̀
16Ẹnikẹ́ni tí ó bá gbàdúrà ìbùkún ní ilẹ̀ náà
17“Kíyèsi i, Èmi yóò dá
18Ṣùgbọ́n ẹ yọ̀ kí inú yín dùn títí láé
19Èmi yóò ṣe àjọyọ̀ lórí Jerusalẹmu
20“Títí láé a kì yóò gbọ́ nínú rẹ̀
21Wọn yó ò kọ́ ilé, wọn yóò sì gbé nínú wọn
22Wọn kì yóò kọ́ ilé fún ẹlòmíràn láti gbé,
23Wọn kì yóò ṣe iṣẹ́ lásán,
24Kí wọn tó pè, èmi yóò dáhùn;
25Ìkookò àti ọ̀dọ́-àgùntàn yóò jẹun pọ̀,