1Nítorí Sioni èmi kì yóò dákẹ́,
2Àwọn orílẹ̀-èdè yóò rí òdodo rẹ,
3Ìwọ yóò sì jẹ́ adé dídán ní ọwọ́ Olúwa,
4Wọn kì yóò pè ọ́ ní ìkọ̀sílẹ̀ mọ́
5Gẹ́gẹ́ bí ọ̀dọ́mọkùnrin tí í gbé ọ̀dọ́mọbìnrin níyàwó,
6Èmi ti fi olùṣọ́ ránṣẹ́ sórí odi rẹ ìwọ Jerusalẹmu;
7àti kí ẹ má ṣe fún òun pẹ̀lú ní ìsinmi
8Olúwa ti búra pẹ̀lú ọwọ́ ọ̀tún rẹ̀
9ṣùgbọ́n àwọn tí ó bá kóórè rẹ̀ ni yóò jẹ ẹ́,
10Ẹ kọjá, ẹ kọjá ní ẹnu ibodè náà!
11Olúwa ti ṣe ìkéde
12A ó sì pè wọ́n ní Ènìyàn Mímọ́,