1“Tẹ́tí sí mi, ẹ̀yin tí ó ń lépa òdodo
2ẹ wo Abrahamu baba yín,
3Dájúdájú, Olúwa yóò tu Sioni nínú
4“Tẹ́tí sí mi, ẹ̀yin ènìyàn mi;
5Òdodo mi ń bọ̀ wá kíkankíkan,
6Gbé ojú rẹ sókè sí àwọn ọ̀run,
7“Ẹ gbọ́ mi, ẹ̀yin tí ó mọ ohun òtítọ́,
8Nítorí kòkòrò yóò mú wọn lá bí aṣọ,
9Dìde, dìde! Kí o sì wọ ara rẹ ní agbára
10Ìwọ kọ́ ni ó gbẹ omi Òkun bí
11Àwọn ẹni ìràpadà Olúwa yóò padà wá.
12“Èmi, àní Èmi, èmi ni ẹni tí ó tù ọ́ nínú.
13tí ìwọ sì gbàgbé Olúwa ẹlẹ́dàá rẹ,
14Àwọn ẹlẹ́wọ̀n tí ń ṣojo la ó dá sílẹ̀ ní àìpẹ́ jọjọ
15Nítorí Èmi ni Olúwa Ọlọ́run rẹ,
16Mo ti fi ọ̀rọ̀ mi sí ẹnu rẹ
17Jí, jí!
18Nínú gbogbo ọmọ tí ó bí
19Àjálù ìlọ́po ìlọ́po yìí ti dé bá ọ—
20Àwọn ọmọkùnrin rẹ ti dákú;
21Nítorí náà ẹ gbọ́ èyí, ẹ̀yin tí a ti ṣẹ́ níṣẹ̀ẹ́,
22Ohun tí Olúwa Olódùmarè yín wí nìyìí,
23Èmi yóò fi lé àwọn apọ́nilójú rẹ lọ́wọ́,