1“Ìránṣẹ́ mi nìyìí, ẹni tí mo gbéró,
2Òun kì yóò pariwo tàbí kígbe sókè,
3Koríko odò títẹ̀ kan ni òun kì yóò fọ́,
4òun kì yóò kọsẹ̀ bẹ́ẹ̀ ni kò ní rẹ̀wẹ̀sì
5Èyí ni ohun tí Olúwa Ọlọ́run wí
6“Èmi, Olúwa, ti pè ọ́ ní òdodo,
7láti la àwọn ojú tí ó fọ́,
8“Èmi ni Olúwa; orúkọ mi nìyìí!
9Kíyèsi i, àwọn nǹkan àtijọ́ ti wáyé,
10Kọ orin tuntun sí Olúwa
11Jẹ́ kí aginjù àti àwọn ìlú rẹ̀ kí ó gbé ohùn wọn sókè;
12Jẹ́ kí wọn fi ògo fún Olúwa
13Olúwa yóò rìn jáde gẹ́gẹ́ bí i ọkùnrin alágbára,
14“Fún ìgbà pípẹ́ ni mo ti dákẹ́ jẹ́ẹ́,
15Èmi yóò sọ òkè ńlá àti kékeré di ahoro
16Èmi yóò tọ àwọn afọ́jú ní ọ̀nà tí wọn kò tí ì mọ̀,
17Ṣùgbọ́n àwọn tí ó gbẹ́kẹ̀lé òrìṣà,
18“Gbọ́, ìwọ adití,
19Ta ló fọ́jú bí kò ṣe ìránṣẹ́ mi,
20Ẹ̀yin ti rí ọ̀pọ̀lọpọ̀ nǹkan, ṣùgbọ́n ẹ kò ṣe àkíyèsí;
21Ó dùn mọ́ Olúwa
22Ṣùgbọ́n àwọn ènìyàn kan nìyìí tí a jà lógun
23Ta ni nínú yín tí yóò tẹ́tí sí èyí
24Ta ni ó fi Jakọbu lélẹ̀ fún ìkógun,
25Nítorí náà ni ó ṣe rọ̀jò ìbínú un rẹ̀ lé wọn lórí,