1Wò ó, ọba kan yóò jẹ nínú òdodo
2Ẹnìkọ̀ọ̀kan yóò jẹ́ bí ibi ìṣápamọ́ kúrò lọ́wọ́ afẹ́fẹ́
3Nígbà náà ni ojú àwọn tí ó rí kò ní padé mọ́,
4Ọkàn àwọn oníwàdùwàdù ni yóò là tí yóò sì yè,
5A kò ní pe òmùgọ̀ ní ọlọ́lá mọ́
6Nítorí òmùgọ̀ sọ̀rọ̀ òmùgọ̀,
7Ibi ni gbogbo ọgbọ́n àwọn ìkà ènìyàn jẹ́,
8Ṣùgbọ́n ọlọ́lá ènìyàn a máa pète ohun ńlá
9Ẹ̀yin obìnrin tí ẹ ti gba ìtẹ́lọ́rùn gidi
10Ní ó lé díẹ̀ ní ọdún kan
11Wárìrì, ẹ̀yin obìnrin onítẹ̀lọ́rùn;
12Ẹ lu ọmú yín fún pápá ìgbádùn náà,
13àti fún ilẹ̀ àwọn ènìyàn mi,
14Ilé olódi ni a ó kọ̀sílẹ̀,
15títí a ó fi tú Ẹ̀mí sí wa lórí láti òkè wá,
16Ẹ̀tọ́ yóò máa gbé ní inú aṣálẹ̀
17Èso òdodo náà yóò sì jẹ́ àlàáfíà;
18Àwọn ènìyàn mi yóò máa gbé ní ibùgbé àlàáfíà,
19Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé yìnyín ti tẹ́jú igbó pẹrẹsẹ
20báwo ni ẹ ó ti jẹ́ alábùkún tó,