1Èyí ni ohun tí Isaiah ọmọ Amosi rí nípa Juda àti Jerusalẹmu.
2Ní ìgbẹ̀yìn ọjọ́
3Ọ̀pọ̀lọpọ̀ ènìyàn ni yóò wá, wọn yóò sì wí pé,
4Òun ó ṣe ìdájọ́ láàrín àwọn orílẹ̀-èdè,
5Wá, ẹ̀yìn ará ilé e Jakọbu,
6Ìwọ ti kọ àwọn ènìyàn rẹ sílẹ̀,
7Ilẹ̀ wọn kún fún fàdákà àti wúrà,
8Ilẹ̀ ẹ wọn kún fún ère,
9Nítorí náà ni a ó ṣe rẹ ènìyàn sílẹ̀
10Wọ inú àpáta lọ,
11Ojú agbéraga ènìyàn ni a ó rẹ̀ sílẹ̀
12Olúwa àwọn ọmọ-ogun ní ọjọ́ kan ní ìpamọ́
13nítorí gbogbo igi kedari Lebanoni, tó ga tó rìpó
14nítorí gbogbo òkè gíga ńlá ńlá
15fún ilé ìṣọ́ gíga gíga
16fún gbogbo ọkọ̀ àwọn oníṣòwò
17Ìgbéraga ènìyàn ni a ó tẹ̀ lórí ba
18gbogbo ère òrìṣà yóò pòórá.
19Àwọn ènìyàn yóò sálọ sínú ihò àpáta
20Ní ọjọ́ náà ni àwọn ènìyàn yóò máa sọ
21Wọn yóò sálọ sínú ihò ìsàlẹ̀ àpáta
22Dẹ́kun à ń gba ènìyàn gbọ́,