1Ègbé ni fún ilẹ̀ tí ó kún fún ariwo ìyẹ́ eṣú,
2tí ó rán àwọn ikọ̀ lórí Òkun
3Gbogbo ẹ̀yin ènìyàn ayé,
4Èyí ni ohun tí Olúwa sọ fún mi:
5Nítorí, kí ìkórè tó bẹ̀rẹ̀,
6A ó fi wọ́n sílẹ̀ fún àwọn ẹyẹ òkè ńlá
7Ní àkókò náà ni a ó mú ẹ̀bùn wá fún Olúwa àwọn ọmọ-ogun