1Ọ̀rọ̀ Olúwa tọ̀ mí wá:
2“Ọmọ ènìyàn, báyìí ni Olúwa Olódùmarè wí sí ilé Israẹli:
3Òpin tí dé sí ọ báyìí,
4Ojú mi kò ní i dá ọ sì,
5“Èyí ni Olúwa Olódùmarè wí:
6Òpin ti dé!
7Ìparun ti dé sórí rẹ,
8Mo ṣetán láti tú ìbínú gbígbóná mi lé ọ lórí
9Ojú mi kò ní i dá ọ sí,
10“ ‘Ọjọ́ náà dé!
11Ìwà ipá ti di ọ̀pá ìwà búburú;
12Àkókò náà dé!
13Nítorí pé òǹtajà kì yóò rí gbà padà
14“ ‘Wọ́n ti fọn ìpè ogun,
15Idà wà ní ìta,
16Gbogbo àwọn tí ó bọ́ nínú wọn yóò sálà,
17Gbogbo ọwọ́ yóò rọ,
18Wọn yóò wọ aṣọ ọ̀fọ̀,
19“ ‘Wọn yóò dà fàdákà wọn sí ojú pópó,
20Wọ́n ń ṣe ìgbéraga pẹ̀lú ohun ọ̀ṣọ́ wọn tí ó lẹ́wà,
21Èmi yóò sì fi àwọn nǹkan wọ̀nyí ṣe ìjẹ fún àjèjì
22Èmi yóò gbójú mi kúrò lára wọn,
23“ ‘Rọ ẹ̀wọ̀n irin!
24Èmi yóò mú kí orílẹ̀-èdè ti ó búburú jùlọ
25Nígbà tí ìpayà bá dé,
26Wàhálà lórí wàhálà yóò dé,
27Ọba yóò ṣọ̀fọ̀,