1Mo ti dé inú ọgbà mi, arábìnrin mi, ìyàwó mi;
2Mo ti sùn ṣùgbọ́n ọkàn mi jí.
3Mo ti bọ́ aṣọ ìgúnwà mi
4Olùfẹ́ mi na ọwọ́ rẹ̀ láti inú ihò ìlẹ̀kùn
5Èmi dìde láti ṣílẹ̀kùn fún olùfẹ́ mi,
6Èmi ṣí ìlẹ̀kùn fún olùfẹ́ mi,
7Àwọn olùṣọ́ tí ń ṣọ́ ìlú rí mi
8Ẹ̀yin ọmọbìnrin Jerusalẹmu, mo bẹ̀ yín
9Kí ni olùfẹ́ rẹ fi dára ju àwọn tókù lọ,
10Olùfẹ́ mi ní ìtànṣán ó sì pọ́n
11Orí rẹ̀ rí bí i wúrà tí ó dára jùlọ
12Ojú rẹ̀ rí bí i ti àdàbà
13Ẹ̀rẹ̀kẹ́ rẹ̀ rí bí ibùsùn tùràrí
14Apá rẹ̀ rí bí i ọ̀pá wúrà,
15Ẹsẹ̀ rẹ̀ rí bí i òpó mabu
16Ẹnu rẹ̀ jẹ́ adùn fún ara rẹ̀